You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Kò ṣe é mà gbọ̀ ọ́
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ti kede pe awọn yoo ṣe iwọde kaakiri Naijiria
tijọba ba tẹsiwaju pẹlu erongba rẹ lati ṣe afikun tariifu owo ina mii
NLC ni kii ṣe asiko yii ti ọwọngogo nnkan gbode ni Naijiria lo yẹ ki ijọba maa gbero lati ṣafikun owo ina.
====================================
Awuyewuye lori aawẹ Ramadan
Bi ti bawo, ki lo fẹ fa awuyewuye lori aawẹ?
Bẹẹ la a bi ni o, ọpọ eeyan lo ti koro oju si bijọba ipinlẹ mẹrin to n samulo ofin Sharia, se gbe ilẹkun ile ẹkọ wọn ati ti aladani ti pa fun osu kan gbako tori aawẹ to n lọ lọwọ.
Iyẹn ma gbẹnutan an, awọn ipinlẹ wo gan na ni?
Idahun s'iberee rẹ wa loju oju opo BBC Yoruba
'''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''
Ọmọ akin o gbọdọ ṣojo, mo fi ara mi silẹ fawọn ajinigbe nigba ti wọn fẹ mu iyawo mi lọ
Olabiyisi Mobolaji Charles tawọn Amotekun doola lọwọ awọn Amotekun lo sọ bẹẹ
Olabiyisi ni miliọnu mẹwaa naira lawọn ajinigbe lawọn o gba kawọn ẹsọ Amotekun to de
Ẹkunrẹrẹ wa lori ikanni BBC.Com/Yoruba