You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Published
Yoruba ni ko sibi to dabi ile ni ẹyẹ n ke, ko si ibi to dabi ilu taa bi ni, bẹẹ si ni ọmọ to sọ ile nu, ti so apo iya kọ.
Bi baba kan se n yangan pe oun n kọ awọn ọmọkunrin oun mẹtẹẹta , ti iyawo rẹ oyinbo bi fun, ni ede abinibi lai naani pe awọn n gbe loke okun, naa ni baba miran to n gbe lorilẹede Naijiria n ge ika jẹ pe oun ko fi ede abinibi kọ ọmọ oun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Maryam Sanda pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lóri ìdàjọ́ ikú
- ''Láìpẹ́, ìjọba ìpínlẹ̀ Eko yóò fi ǹkan tó dára míì rọ́pò Kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kadà''
- Ìhàlẹ̀ lásán ní NURTW ń ṣe torí pé a dínà owó tí wọn ń kó sápò - Ìjọba Ọyọ
- Kìí ṣe torí gbígba àmì ẹ̀yẹ ni ọmọ wa ṣe kú, a dúpẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tẹ rántí rẹ̀ - Ẹbí Adadevoh
- Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
Eyi lo ni o jẹ ko padanu isẹ olowo nla to yẹ ko ri gba lẹyin to jade nileẹkọ.
Fidio yii kọ ni lẹkọ pupọ, ẹ gbọ ọrọ lẹnu awọn to n poungbẹ agbelarugẹ asa, kẹ si kọgbọn.
- Lekan Balogun, dá ₦6.5m owó oyè tó gbà lọ́wọ́ òkú padà, àwọn ará ilé rẹ̀ ń bèèrè - Olúbàdàn
- Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun
- Owó àwọn aṣòfin kò pọ̀jù, iṣẹ́ kàbàtì tí wọn ń ṣe ju owó oṣù wọn lọ - Buhari
- Kò síbi tó dàbí ilé, tìlù-tìfọn ni wọ́n fi kí Anthony Joshua tó bẹ ìlú rẹ̀, Ṣágámù wò káàbọ̀
- Àbòsí ló wà níbẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko ò bá ṣe Amotekun- Bode George