BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Aabo orile-ede
Àwọn agbébọn tún ṣèkọlù sí Eruku ní Kwara, jí àgbẹ̀ kan gbé lọ lẹ́yìn ìkọlù ilé ìjọ́sìn CAC
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ṣé lóòótọ́ ní ayẹta Yorùbá wà, àwọn wo ló le lò ó, kí ni èèwọ̀ rẹ̀ àti ìdí tó fi lè kùnà?
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Abẹ ìsẹjọba rẹ gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ni ìgbésùnmọ̀mí ti bẹ̀rẹ̀- Iléeṣẹ́ Ààrẹ fèsì padà fún Obasanjo
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Agbébọn jí obìnrin tó fẹ́ ṣe ìgbéyàwó láàárọ̀ òní, ọ̀rẹ́ rẹ̀, àtàwọn mẹ́jọ míì gbé lọ
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Àwọn jàndùkú agbébọn tún ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Kerubu (C&S) ní Kogi, jí pásítọ̀ àti ìyàwó rẹ̀ pẹ̀lú àwọn èèyàn míì gbé lọ
30 Bélú 2025
Ìkọ́ aláàbò dóòlà ọ̀dọ́bìnrin méjìlá tí ajínigbé jí gbé ní Borno
30 Bélú 2025
Wo onírúurú ikọ̀ agbésùnmọ̀mí, ajínigbé àti ẹlẹ́yàmẹ̀yà mẹ́sàn án tó ń da ètò àbò Naijiria rú
28 Bélú 2025
7:11
Fídíò,
Kí ló fà á táwọn agbébọn ṣe rọgba yí ìpínlẹ̀ Kwara ká àti ipa tó ní lórí aráàlú?
, Duration 7,11
28 Bélú 2025
Àwọn gómìnà Gùùsù Naijiiria ṣe ìpàdé l‘Ogun, wo kókó ohun mẹ́fà tí wọn ń fẹ́
28 Bélú 2025
Kókó ohun mẹ́jọ tí yóò ṣẹlẹ̀ lásìkò yìí pẹ̀lú ìkéde pàjáwìrì lẹ́kà ààbò tí Tinubu ṣe àti bó ṣe kàn ọ́
27 Bélú 2025
Ìdúnàádúrà pẹ̀lú agbébọn jẹ́ ìwà ọ̀dàlẹ̀ sọ́mọ Nàíjíríà, kò sí ibi tó ti so èso rere ní àgbáyé, àbàmọ̀ ló ń gbẹ̀yìn rẹ̀ - Àwọn aṣòfin kan yarí
27 Bélú 2025
Akẹ́kọ̀ọ́ mọ̀kànlá nínú 303 tilé ẹ̀kọ́ St Mary Catholic ní Niger bọ́ lọ́wọ́ agbebọn, bí Gómìnà Kebbi ṣe fẹ́ fa akẹ́kọ̀ọ́ 24 tó dé láti ọ̀dọ̀ ajínigbé, lé òbí wọn lọ́wọ́
26 Bélú 2025
Kí ni ìtúmọ̀ ìlànà 'non-kinetic' tí ìjọba ní òun fi dúnàádúrà gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kebbi àti olùjọ́sìn Eruku lọ́wọ́ àwọn ajínigbé?
26 Bélú 2025
Ẹ̀yin ológun, ẹ gbákoso, rọ̀gbà yí àwọn igbó ọba tó wà ní Kwara, Niger àti Kebbi ká, ẹ gba àwọn tó wà ní ìgbèkùn ajínigbé kalẹ̀ - Tinubu
26 Bélú 2025
Nàìjíríà lọ́ bá Amẹ́ríkà ṣèpàdé lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ tí Trump pariwo rẹ̀, kókó àbọ̀ wọn rèé
26 Bélú 2025
Kókó ohun mẹ́wàá táwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá ń bèèrè níbi ìpàdé pàjáwìrì wọn
25 Bélú 2025
Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tíwà ìjínigbé tí gogò ní Nàíjíríà, kí ló dé tí ìjọba kò ṣe tí ì rẹ́yìn rẹ̀?
25 Bélú 2025
"Àlàyé rèé lórí bí ọmọ mi, ọmọ ọdún mẹ́fà ṣe bọ́ lọ́wọ́ ajínigbé ní Papiri àmọ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ méjì sì wà lọ́dọ̀ agbébọn"
24 Bélú 2025
Akẹ́kọ̀ọ́ 50 sá wálé lákàtà ajínigbé nínú àwọn 315 tí wọ́n jí gbé nípìnlẹ̀ Niger
23 Bélú 2025
Ìjọba ìpínlẹ̀ Borno ya ọjọ́ Ajé ọ̀sẹ̀ yìí sọ́tọ̀ fún ààwẹ̀ àti àdúà gbígbà
23 Bélú 2025
Ìjọba àpapọ̀, àwọn ìpínlẹ̀ gbé ilé ẹ̀kọ́ tìpa nítorí ìkọlù àwọn ajínigbé
22 Bélú 2025
Ìwọ̀nyí ni orílẹ̀èdè mẹ́wàá ní Afrika tí wọ́n ya òbítíbitì owó sọ́tọ̀ fún ètò àbò wọn
22 Bélú 2025
Orílẹ́èdè Afirika mẹ́wàá tí ìjọba ti náwó jùlọ lórí ètò ààbò lọ́dún 2025
22 Bélú 2025
Ìṣájú
Page
10
nínú
40
1
7
8
9
10
11
12
13
40
Tókàn