BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Orilẹede Naijiria
Àwọn gbajúmọ̀ t'áwọn ọmọ Naijiria wá ìròyìn nípa wọn jùlọ lórí Google lọ́dún 2025
15 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Agbébọn tún kọlu ṣọ́ọ̀ṣì ní Kogi, pa èèyàn, jí ọ̀pọ̀ míràn gbé
15 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Dangote fárígá, Ó ní kí ọ̀gá àjọ alámójútó epo rọ̀bì wá sọ bó ṣe rí $5 mílíọ̀nù tó fi rán ọmọ mẹ́rin lọ kàwé lókè òkun
15 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
3:56
Fídíò,
Ọba ìlú Epe Ekiti fi àṣẹ ìṣẹ̀mbáyé ṣépé fáwọn ọmọ ìlú, ìlú bá fárígá fìbínú lé nílùú
, Duration 3,56
15 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ilé ìfowópamọ́ yóò máa bèèrè káàdì owó orí láti oṣù tó ń bọ̀, ìdí abájọ rèé
13 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Àlàyé rèé lórí ohun tó rọ̀ mọ́ ikú igbákejì gómìnà ni Bayelsa, Lawrence Ewhrudjakpo, àti bí ọ̀pọ̀ èèyàn ṣe ń ṣe ìdárò rẹ̀
12 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ipa wo ni ìgbésẹ̀ Tinubu láti kó ọmọ ogun lọ Benin yóò ní lórí ìgbógun ti agbébọn ní Naijiria?
10 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Wo àwọn gómìnà PDP tó ti fi ẹgbẹ́ sílẹ̀ àti àwọn tó ṣẹ́kù
10 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ológun Nàìjiríà kò lè borí àwọn agbébọn, ìdí rèé tí mo fi ní kí ìjọba dúnàádúrà pẹ̀lú wọn - Sheikh Gumi
10 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ilé aṣòfin ní kí Tinubu fi ọmọ ogun ránṣẹ́ sí Benin Republic
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Agbègbè méjì dojú ogun kọra wọn, ẹ̀mí bọ́, ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò, ìjọba kéde òfin kónílé-gbélé
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Àwọn ipa tí ìgbésẹ̀ mímú ológun mọ̀kànlá sáhàámọ́, gbẹ́sẹ́ lé bàálù le è ní bí Nàíjíríà ṣe fèsì lórí ìdí tí bàálù rẹ̀ fi balẹ̀ lójijì ní agbègbè Sahel
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Agbébọn tún kọlu ilé ìjọ́sìn, wọ́n pa ìyàwó pásítọ̀, jó ọ̀pọ̀ ọkọ̀ níná, ṣe ọ̀pọ̀ èèyàn lèṣe
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ìjọba àpapọ̀ kéde ìdáǹdè akẹ́kọ̀ọ́ 100 nínú àwọn tí wọ́n jí gbé ní St Mary Catholic, Papiri
8 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Kí nídìí táwọn Ajẹ́rìí Jèhófà kìí fí gba ẹ̀jẹ̀ bí obìnrin tó ní àìsàn jẹjẹrẹ ṣe kọ̀ láti gba ẹ̀jẹ̀
8 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ohun ìyanu rere ń bọ̀ nínu ìjọba Tinubu, gbogbo ọ̀tá rẹ̀ ni ojú yóò tì - Remi Tinubu
8 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Kí ló dé tí APC yọ Omisore, Omoworare àtàwọn mí-ìn kúrò nínú ìbò abẹ́lé sípò gómìnà Osun?
6 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ajínigbé jí àwọn ọmọ ilẹ̀ China méjì gbé lẹ́nu isẹ́ ní Kwara
6 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ìjọba gbọ́dọ̀ ní àkójọpọ̀ orúkọ gbogbo aráàlú lórí ẹ̀rọ kọ̀mpútà tó bá fẹ́ rẹ́yìn ìgbésùnmọ̀mí - Christopher Musa
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
"Òfin Sharia wà lára nǹkan tó ń fa ìṣekùpani Kristẹni ní Naijiria"
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Báǹkì àgbà ilẹ̀ wa, CBN, mú àdínkù bá owó gbígbà síta
4 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Kí ló dé tí ìjọba US ṣe fẹ́ dènà físà àwọn ọmọ Naijiria kan, òṣìṣẹ́ ìjọba àti ẹbí wọn?
4 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Kókó àbájáde ìwádìí àwọn aṣòfin Amẹrika lórí ọ̀rọ̀ tí Trump sọ pé ìpanirun àwọn Kristẹ́nì ń ṣẹlẹ̀ ní Naijiria
3 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Edo ní kí ìyàwó Tuface, Natasha Osawaru, wáá ṣàlàyé ara rẹ̀, ìdí rèé
3 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ìṣájú
Page
16
nínú
40
1
13
14
15
16
17
18
19
40
Tókàn