BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipinlẹ Oyo
CAN gbé ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ orúkọ àwọn èèyàn tí ajínigbé gbé nílé ẹ̀kọ́ mẹ́ta nípínlẹ̀ Oyo jáde, bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ àti àdúrà
21 Èbibi 2026
Wo àwọn ìpínlẹ́ àti ìlú tí àwọn agbébọn ti kọlù nílẹ̀ẹ Yorùbá
20 Èbibi 2026
3:22
Fídíò,
Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele
, Duration 3,22
20 Èbibi 2026
Ṣé lóòótọ́ làwọn agbébọn tún yawọ ìlú Ogbomoso? Àlàyé rèé
19 Èbibi 2026
Ọlọ́pàá ṣàlàyé bí àwọn alamí ṣe ran àwọn ajínigbé tó kọlu iléẹ̀kọ́, jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Oyo lọ́wọ́
19 Èbibi 2026
Gómìnà Seyi Makinde ní ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ṣetán láti jíròrò pẹ̀lú àwọn agbébọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́ gbé kí wọ́n lè tètè padà wálé
19 Èbibi 2026
Àwọn aṣojú-ṣòfin tó wà níjọba wọlé ìbò abẹ́nú APC ní ìpínlẹ̀ Oyo, àwọn alátakò fọnmú pé Tinubu ń ṣàtìlẹ́yìn fún wọn
16 Èbibi 2026
Agbébọn tún yabo ilé ẹ̀kọ́ méjì ní Borno, jí ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ gbé lọ
16 Èbibi 2026
Làásìgbò bẹ́ sílẹ̀ lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC Oyo, wọ́n ba ilé ẹgbẹ́, dúkìá àwọn olùdíje sípò gómìnà jẹ́
15 Èbibi 2026
Gómìnà Seyi Makinde kéde pé òun yóò dupò ààrẹ Naijiria ni 2027
14 Èbibi 2026
Àwọn ọmọ Nàìjíríà máa fi ojú àwọn olóṣèlú dánrin níbi ètò ìdìbò tó ń bọ̀ - Seyi Makinde
14 Èbibi 2026
Ọ̀pọ̀ èrò n‘Ibadan fẹ̀sùn ajínigbé kan Dókítà kan, wọ́n fẹ́ lú ú pa, dáná sun ọkọ̀ rẹ̀, ọ̀pẹ́ ọlọ́pàá tó dé sásìkò
13 Èbibi 2026
Kí ló dé tí ọ̀pọ̀ àwọn tó ń bá Gómìnà Seyi Makinde ṣiṣẹ́ níjọba ìpínlẹ̀ Oyo ń kọ̀wé fipò sílẹ̀?
9 Èbibi 2026
Èmi ò sọ̀rọ̀ tàbùkù Olubadan o, ọmọ ni mo jẹ́ sí Ọba Rashidi Ladọja - Bayọ Adelabu sọ̀rọ̀ síta lẹ́yìn tí wọ́n ní ó sọ̀kò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ s'Olubadan nítorí òṣèlú
4 Èbibi 2026
Ààrẹ Tinubu ló ni àsìkò ti tó fún mi láti lọ dupò gómínà Oyo- Adelabu
3 Èbibi 2026
Ẹbí ọlọ́kadà tó kú n'Ibadan lẹ́yìn táwọn ọlọ́pàá dá a dúró ké gbàjarè, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàlàyé nǹkan tó ṣẹlẹ̀
2 Èbibi 2026
4:29
Fídíò,
Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan
, Duration 4,29
24 Ìgbé 2026
Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan
24 Ìgbé 2026
Erin kọlu ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Oyo, pa èèyàn kan, ẹlòmíì di àwátì
24 Ìgbé 2026
Gbọin-gbọin ni a wà lẹ́yìn Makinde bí òkè, àhesọ ọ̀rọ̀ lásán n'ìròyìn tó ní a fẹ́ yọ ọ́ nípò – Ilé Aṣòfin Oyo
23 Ìgbé 2026
Mínísítà fọ́rọ̀ ohun àmúsagbára Adebayo Adelabu ṣàlàyé ìdí tó fi kọ̀wé fipò sílẹ̀
23 Ìgbé 2026
A ti yanjú aáwọ̀ láàárín Makinde àti Olubadan-Ìgbìmọ̀ ọmọ Ibadan
20 Ìgbé 2026
Ọba kì í ṣe òṣèlú, Olubadan, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ kẹ́ ẹ má baà mú àrífín wá - Balogun Olubadan
18 Ìgbé 2026
"Ẹ̀yin ọ̀dọ́ tí ẹ̀ ń kún pé bí Toun Soetan ṣe ń kọrin ń di yín lọ́wọ́ láti dárà nínú ìjọ, ó ti lọ, ẹ wá dárà yín ká rí i"
17 Ìgbé 2026
Ìṣájú
Page
2
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
8
40
Tókàn