BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ẹsin
4:42
Fídíò,
Ọlọ́run táwọn mùsùlùmí àtàwọn onígbàgbọ́ ń sìn pẹ̀lú àwọn òrìṣà tiwa lẹgbẹ́ - Alaṣẹ Ijọ Orunmila
, Duration 4,42
15 Ọ̀wàrà 2024
Ọwọ́ kò tíì tẹ Alfa Saheed Shittu, ní ilé ẹjọ́ bá ju ọmọṣẹ rẹ̀ kan sí ẹ̀wọ̀n n'Ilorin
12 Ọ̀wàrà 2024
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ìlú kan wà ní Naijiria, níbi tí wọ́n ti ń ju ọmọ sígbó nítorí pé 'àjẹ́ ni wọ́n'?
10 Ọ̀wàrà 2024
Ẹ̀yin tí pásítọ̀ yín kò bá bèèrè fún ìdámẹ́wàá, ẹ máa dá ọrẹ àmọ́... - Adeboye
6 Ọ̀wàrà 2024
8:17
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ làwọn márùn ún kú lẹ̀yìn tí wọ́n jẹ ìpèsè ní ṣọ́ọ̀ṣì kan? Ohun tí ìwádìí wa fi múlẹ̀ nìyí
, Duration 8,17
3 Ọ̀wàrà 2024
Ìjàmbá ọkọ̀ pa Mùsùlùmí bí 40 lásìkò tí wọ́n ń rìnrìn àjò lọ fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Anọbi
17 Owewe 2024
5:17
Fídíò,
Sheik L'Agbaji sọ̀rọ̀ lórí fídíò òun àti Wòólì Genesis tó fa awuyewuye lórí ayélujára
, Duration 5,17
16 Owewe 2024
Mi ò forúkọ NAFDAC bojú láti ta omi ìyanu - Pásítọ̀ Jeremiah Fufeyin fèsì
9 Owewe 2024
Ìdí tí Soun Ogbomoso fi yan ìmáàmù ààfin tuntun rèé
5 Owewe 2024
Ọlọ́pàá pa lára àwọn ọmọ ìjọ wa nílùú Abuja - Shiites
26 Ògún 2024
Kí ló dé tí àwọn èèkàn akọrin ẹ̀mí kò fi yọjú sí ibi ètò ìsìnkú Aduke Gold? Mọ́lẹ̀bi ṣàlàyé
24 Ògún 2024
“Gbogbo agbára àwa oníṣẹ̀se la máa fi bá Ọba tí kò bá fi àyè gba ìsẹ̀se jà láti le kúrò lórí ìtẹ́”
20 Ògún 2024
6:09
Fídíò,
Kò sí oníṣẹ̀ṣe tó ń pe Ògún, Èṣù ní Ọlọ́run bí àwọn ẹlẹ́sìn kan ṣe ń yára sọ ènìyàn di ọlọ́run wọn – Ifaleke, adarí ìjọ Ọ̀rúnmìlà
, Duration 6,09
20 Ògún 2024
Àlàyé ohun tó fa wàhálà ní ilé ìjọsìn l'Abuja, tí ọlọ́pàá fi fi tajútajú 'tear gas' tú ìsìn ká
19 Ògún 2024
“Ọdún méjìlá gbáko ló gbà wá kí àjọ UNESCO tó fòntẹ̀ lu ọdún Sango àgbáyé”
17 Ògún 2024
ICPC ṣàlàyé ìdí tó fi gbé àwọn òṣìṣẹ́ àjọ tó wà fún ìrìnàjò sílẹ̀ mímọ́
13 Ògún 2024
1:51
Fídíò,
Àwọn ọlọ́pàá Sharia ń fi tipá gbé àwọn obìnrin tí kò lo Hijab sí àhàmọ́, ọ̀rọ̀ di tilé ẹjọ́
, Duration 1,51
13 Ògún 2024
Ìdí rèé tí mo fi kúnlẹ̀ níwájú Pásítọ̀ Adeboye - Soun Ogbomoso sàlàyé
13 Ògún 2024
B‘áwọn ṣọ́ọ̀ṣì bá ń wáàṣù àláàfíà àti ìtẹpámọ́ṣẹ́ dípò ọrọ̀ òjijì, Nàíjíríà yóò dìde padà - Osinbajo
12 Ògún 2024
Ọba tó bá fẹ́ fọnrere ẹ̀sìn Islam àti Krìstẹ́nì lórí oyè, kó lọ sí Mecca tàbí Jerusalem – Olówu ti ìlú Kuta
10 Ògún 2024
Ìjọba gbe ṣọ́ọ̀ṣì 4,000 tìpa, ìdí abájọ rèé
4 Ògún 2024
Kí ni ẹ̀sìn rẹ sọ nípa ìwọ́de àti ṣíṣe ìfẹ̀hónúhàn?
2 Ògún 2024
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ètò orin kíkọ, èèyàn mẹ́sàn-án jáde láyé
28 Agẹmo 2024
Kí ló fa ariwo, tí ọ̀pọ̀ èèyàn sì faraya torí Orò tí yóò jáde lásìkò ìwọ́de ebi ń pa wá?
25 Agẹmo 2024
Ìṣájú
Page
9
nínú
35
1
6
7
8
9
10
11
12
35
Tókàn