BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ehonu
Àwọn alákòsóo APC l‘Abuja ti gbàbọ̀dè, APC l‘Oyo sì le kùnà ìbò gómìnà - Adeseun
8 Èrèlè 2022
"Á lọ yíká gbogbo ilẹ̀ Yorùbá láti bèèrè fún ìdáǹdè Sunday Igboho"
29 Sẹ́rẹ́ 2022
Osun la fẹ́ kí ìgbẹ́jọ́ ikú Timothy Adegoke ti wáyé, kìí ṣe Abuja - Mọ̀lẹ́bí yarí
28 Sẹ́rẹ́ 2022
Ìdìbò láti yan olùdíje APC fún ipò gómìnà l'Ekiti ń parí lọ, àmọ́...
27 Sẹ́rẹ́ 2022
Kí ló pa akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ Nàíjíríà tó kú lọ́jọ́ kejì tó dé ilé ẹ̀kọ́ ní Ukraine?
27 Sẹ́rẹ́ 2022
Mo fẹ́ fojú rí Sunday Igboho ní àhámọ́ tó wà, kò sì ní bọ́ níbẹ̀ - Seriki Fulani
24 Sẹ́rẹ́ 2022
''A kò ní dẹ́kun ìfẹ̀hònúhàn àyàfi tí ìjọba àtàwọn aláṣẹ FUTA bá gbé ìgbésẹ̀ lórí ètò àbò àwa akẹ́kọ̀ọ́''
17 Sẹ́rẹ́ 2022
5:29
Fídíò,
Ipò obìnrin nínú òṣèlú kò rọrún ní Nàìjíríà rárá- Senato Olujinmi Biodun
, Duration 5,29
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2021
Ọ̀kùnrin to tú àṣírí ohùn Olóyè Sunday Igboho lórí fóònù ti bọ́ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Cotonou
17 Ọ̀pẹ̀̀ 2021
Òfo ni 'White Paper' Sanwo-Olu kò sí ǹkan tó n jẹ́ bẹ́ẹ̀ lábẹ́ òfin - Adegboruwa
3 Ọ̀pẹ̀̀ 2021
Àwọn ọ̀dọ́ Eruwa ṣe ìwọ́de lórí ikú Timothy Adegoke tó kú sílé ìtura ní Ife
3 Ọ̀pẹ̀̀ 2021
"Ajínigbé, ẹ sá kúrò nílẹ̀ Yorùbá, àwa Agbekoya ti jáde"
2 Ọ̀pẹ̀̀ 2021
A kò faramọ́ àbájáde ''Endsars Panel Report'', kò sí ẹni tó kú ní Lekki Tollgate sẹ́ẹ̀, "White paper" wa rèé - Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2021
3:27
Fídíò,
Ilé tẹ́ẹ rò pé ìjọba Eko fún wa, wọ́n rẹ́ǹtì rẹ̀ ni, a kò tíì rí N1Miliọ̀nù kankan di àsìkò yìí - Iya Jumoke
, Duration 3,27
30 Bélú 2021
5:46
Fídíò,
Lai Muhammed ló ń mú kíjọba àpápọ̀ kọ ẹ̀yìn síbi táyé kọjú sí - EndSARS
, Duration 5,46
27 Bélú 2021
Awuyewuye bẹ́ sílẹ̀ lórí ìlànà ìsìnkú Baba Suwe, àwọn Alfa yarí
25 Bélú 2021
Tówẹ́ẹ̀lì ni bàbá mi ró mọ́ ìdí nígbà tí àwọn sọ́jà wọlé mu lọ - Ọmọ Akintunde
24 Bélú 2021
Jàndùkú kọlù mi, gé mi lára bíi olè torí mo jẹ́rìí tako ìjọba níbi ìwádìí ìpànìyàn Endsars Lekki''
24 Bélú 2021
Buhari, fi Sunday Igboho sílẹ̀, kí ìṣọ̀kan le padà sí Naijiria - Oluwo
23 Bélú 2021
Ìjọba fẹ́ pa mí torí àbọ̀ ìwádìí ìkú olùwọ́de EndSARS ní Lekki - Adegboruwa figbe ta
22 Bélú 2021
8:16
Fídíò,
Òbí mẹ́ta ń banújẹ́ torí bí ọlọ́pàá ṣe gbé àwọn ọmọ wọn tó kópa nínú ìwọ́de EndSARS pamọ́ láti ọdún kan sẹ́yìn
, Duration 8,16
22 Bélú 2021
Ìjọba Eko fi ẹ̀bùn ńlá tọrẹ fún ìyá ọmọ tó kú lásìkò ìwọ́de Yoruba Nation l‘Ojota
21 Bélú 2021
'Irọ́ ńlá lẹ pa, Lai Mohammed ò kó ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate'
17 Bélú 2021
Ọnà ayédèrú ní wọn gbà gbé àbájáde ìwádìí Endsars tàwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ jáde - Ọgágun Irabor
17 Bélú 2021
Ìṣájú
Page
16
nínú
28
1
13
14
15
16
17
18
19
28
Tókàn