BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Ojú ewé to wà yìí,
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojú ewé to wà yìí,
Fídíò
Fídíò
3:16
Fídíò,
Hauwa Lawal, gbajúmọ̀ lórí ayélujára dá sí 'Sóo láyà?'
, Duration 3,16
24 Sẹ́rẹ́ 2026
3:48
Fídíò,
Wo òkúta tó sọ ìlú Ilorin lórúkọ tó ń jẹ́
, Duration 3,48
23 Sẹ́rẹ́ 2026
1:52
Fídíò,
Kí nìdí tí oríṣiríṣi oúnjẹ máa ń wu aláboyún jẹ: ojúkòkòrò ni tàbí àtẹnujẹ? Àlàyé rèé
, Duration 1,52
22 Sẹ́rẹ́ 2026
4:26
Fídíò,
Wo bí ìlú Omu Aran ṣe bẹ̀rẹ̀, tan pẹ̀lú Ìgbómìnà nínú ìtàn Yorùbá
, Duration 4,26
21 Sẹ́rẹ́ 2026
2:28
Fídíò,
Ọbẹ̀ Osi, àràmàǹdà ọbẹ̀ tí wọ́n ń fi wákàtí mẹ́rin, tàbí jùbẹ́ẹ̀ lọ sè
, Duration 2,28
20 Sẹ́rẹ́ 2026
"Nítorí àwọn ọmọ mi tí wọ́n jí gbé ni mo ṣe darapọ̀ mọ́ iṣẹ́ ọlọ́pàá"
20 Sẹ́rẹ́ 2026
4:45
Fídíò,
Wasiu Ayinde K1 kò lẹ́tọ̀ọ́ sí àpèrè Awujale lọ́tẹ̀ yìí, Àwọn afọbajẹ ilẹ̀ Ijebu ṣàlàyé ìlànà tí wọ́n máa fi yan Awujale tuntun
, Duration 4,45
19 Sẹ́rẹ́ 2026
4:37
Fídíò,
Wo bàbá àgbà tó ń gun ọ̀kadà polongo bí a ṣe lè tọ́ ọmọkùnrin yanjú lágbàáyé
, Duration 4,37
16 Sẹ́rẹ́ 2026
1:06
Fídíò,
Mọ̀ nípa èròjà aládùn tí wọ́n fi ń rọ́pò ṣúgà nínú oúnjẹ́, tó ń ṣe àkóbá fún àgọ̀ ara
, Duration 1,06
15 Sẹ́rẹ́ 2026
3:49
Fídíò,
Orúkọ ọkọ mi ló wà níbi gbogbo dúkìá tí a ní, àmọ́ mi ò ri rò-Kemi Fajana,ìyàwó tó bá ọkọ rẹ̀ da òwò pọ̀
, Duration 3,49
13 Sẹ́rẹ́ 2026
3:51
Fídíò,
Ṣíṣe bíi Quadri kò ki í ṣe ohun tí mo ní lọ́kàn tẹ́lẹ̀, ìdí rèé- Taooma
, Duration 3,51
12 Sẹ́rẹ́ 2026
3:57
Fídíò,
Ẹ bá mi rọ Ọba Ghandi kó má tún ìtàn Ògbórí Ẹlẹ́mọ̀ṣọ́ yà- Ẹda Onile Ola
, Duration 3,57
6 Sẹ́rẹ́ 2026
3:19
Fídíò,
Àìrí iṣẹ́ ṣe kọ́ ló sọ mi di ẹni tó ń ṣẹ̀fẹ̀ lórí ayélujára- Folagade Banks
, Duration 3,19
5 Sẹ́rẹ́ 2026
'Ayé ò níì padà já a yín sí ìhòhò lọ́dún tuntun'
4 Sẹ́rẹ́ 2026
1:20
Fídíò,
"Ẹní bá rokúròyín, mo wíi lórúkọ Olúwa, ọ́sán gangan làá gbọ̀'kú aró, òjijì làfọ̀n wọ̀ …"– Àgbà òṣèré tíátà, Lere Paimo wúre ọdún
, Duration 1,20
3 Sẹ́rẹ́ 2026
3:02
Fídíò,
A ò ní ṣìrìn lọ́dùn tuntun -Imam ìjọ Shafaudeen in Islam, Sabit Olagoke gbàdúrà fáwọn ọmọ Nàìjíríà
, Duration 3,02
2 Sẹ́rẹ́ 2026
1:49
Fídíò,
'Lọ́dún 2026, ẹyẹ á ké bí ẹyẹ, ọmọ èèyàn á fọhùn bí ọmọ èèyàn', Soun Ogbomosho, Ọba Ghandi Olaoye ṣe ìwúre ọdún
, Duration 1,49
1 Sẹ́rẹ́ 2026
Wo bí o ṣe lè gba nọ́mbà ìdánimọ̀ owó orí, TIN rẹ láì dàmú jìnnà
31 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
1:48
Fídíò,
Òfin tí ìjọba Nàìjíríà fi de ọtí inú ọ̀rá, Pẹlẹbẹ bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ tó gbẹ̀yìn lọ́dún 2025, ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa rẹ̀ nìyí
, Duration 1,48
29 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Kí ló ń jẹ́ Eyo, níbo ló ti wá sílú Eko, àwọn wo ló ń gbé e, kí sì ni èèwọ̀ rẹ̀?
27 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
1:35
Fídíò,
Kí ló ń mú káwọn ọmọdébìnrin tètè gúnmú, ṣe nǹkan oṣù lásìkò yìí?
, Duration 1,35
25 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Benin yóò gbẹ̀san lára Super Eagles nínú ìdíje AFCON tó ń lọ lọ́wọ́, torí bí Nàìjíríà kò ṣe jẹ́ ká lọ fún ìdíje 2026 World Cup - Olaitan Junior
24 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
5:37
Fídíò,
"Àwọn dókítà yọ kíndìnrín mi láì sọ fún mi, oṣù kẹta rèé tí mi ò lè tọ̀, ṣe ni inú mi ń wú tí mo bá jẹun kékeré"
, Duration 5,37
23 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
5:19
Fídíò,
Ìyá mi máa ń fi mí ṣe yẹ̀yẹ́ pé mi ò lè jọba nítorí n kò kọlà, torí náà, n kò rí ara mi bíi ẹni tó máa jọba - Soun Ogbomoso
, Duration 5,19
22 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ìṣájú
Page
7
nínú
40
1
4
5
6
7
8
9
10
40
Tókàn