You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Akẹ́kọ̀ọ́ FGC Yauri mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n nígbà t'awọn ológun àti ajínigbe kojú ará wọ́n
Awọn to ba BBC sọrọ sọ pe ninu ikọlu to waye laarin awọn agbebọn yi ati ọmọogun Naijiria ni awọn ọmọ yi ti padanu ẹmi wọn.
Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ tí ń lọ lọ́wọ́
Yetunde Olugbenga and Yemisi Oyedepo
Wo àwọn òrékelẹ́wà tí yóò ṣe opó lẹ́yìn Aláàfin Oba Adeyemi tó papòdà
Okùnrin tó so àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mọ́lẹ̀ bíi ewúrẹ́, tó sì nà wọ́n rí ẹ̀wọ̀n ogún ọdún he
'Èèwọ̀! Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́'
Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé
Ta ni Yorùbá ń pè ní Abọ́bakú?
Ààrẹ Buhari, Ooni Ile Ife, Obasanjo kẹ́dùn Alaafin Oyo tó wàjà
Wo àwọn ǹkan tí o kò mọ̀ nípa Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò tó wàjà
Àlè kun abilékọ bíi ẹran ọ̀yà láti fi ṣe òògùn owó, ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ
Ẹ wo ọ̀pọ̀ ìgbà tí àwọn òṣèré fíìmù Yorùbá ti gbé àwọn olólùfẹ́ wọn ní ‘handicap'
Ìdásílẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ ló le yanjú ìṣòro ètò ààbò tó mẹ́hẹ - Obasanjo
Wo iye tó o san to bá fẹ́ lọ sí Hajj ọdún yìí
Ǹjẹ́ o rántí ìyá àtàwọn ọmọ olójú búlúù tí ọkọ pa tì n'Ilorin torí ojú? Wo bó ṣe bẹ̀bẹ̀ padà tí ìfẹ́ gbá rìfáàsì
Òṣìṣẹ́ ìjọba gba àṣẹ lọ rọọ́kún nílé nítorí ìròyìn òfégè ìkú nípa Gómìnà Akeredolu
Oluwo, tètè yípadà nídìí títàbùkù Yorùbá tori ewe ń bẹ̀, òògùn wà
Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo
Ọwọ́ tẹ àwọn afurasí ajínigbé méjì ní ìlú Ife
Àwọn ọ̀dọ́ ló leè gba Naijiria là kúrò ní oko ẹrú –Imam Akeugbagold
Fídíò Chrisland, ikú Sylvester Oromoni, àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ gbankọ gbì tó wáyé láwọn ilẹ ẹ̀kọ́ girama
Kìí ṣe ẹ̀bi wa wí pé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣe àṣemáṣe - ile ẹ̀kọ́ Chrisland