Adebayo Adelabu,ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Penkẹlẹmẹsi ni orúkọ̀ tí àwọn èèyàn máa ń pè Adebayo Adelabu èyí tó jẹ́ orúkọ ìnagijẹ Bàbá rẹ̀ tó jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká olóṣèlú nípínlẹ̀ Ọyọ nígbà kan rí.
- Wọ́n bíi ní ọjọ́ keèjìdínlọ́gbọ̀n, oṣù kẹẹ̀sàn án, ọdún 1970 - Ó jẹ́ igbákejì Gómìnà, Bánkì àpapọ̀ Nàìjíríà (CBN)- Ọmọ agbègbè Kudẹti ní ìlú Ibadan - Akẹkọgboye ninu imọ Iṣiro owo lati fasiti Obafemi Awolowo ni. - Ọmọ ẹgbẹ ajọ Institute of Chartered Accountants of Nigeria (ICAN) nii ṣe.