Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Faakaja laarin ọlọpaa ati ileeṣẹ ọmogun oju omi
Ki lo dawọn pọ?
Ijoba ipinlẹ Ọsun lo maa fẹsun kan ileeṣẹ ọlọpaa pe wọn ṣekọlu sọmogun oju omi kan
To fọwọ omi mawọn janduku to n da ilu tori wọn fẹ gba gareeji ọkọ n'Ile-Ife
Ki ni ileeṣẹ ọlọpaa wa sọ?
Idahun sibeere rẹ wa loju opo wa
''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''
A gbọdọ mọ ohun to ṣokunfa iku ọmọ wa
Ta lo tun ku?
Ijọba apapọ lo n pe fun iwadii kikun lori bi ọmọ Naijiria mi-in tun ṣeku sọwọ awọn ọlọpaa lorilẹede South Africa
Ọgbọnjọ oṣu Kẹfa to kọja yii ni South Africa fi gbedeke si
fawọn ajeji lati filuu wọn silẹ
Ẹkunrẹrẹ wa loju opo wa
''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''
Njẹ ẹ ti gbọ pe BBC Yoruba yoo ṣe ijiroro fawọn oludije sipo gomina nipinlẹ Osun
Nibi ijororo yii ni Gomina Ademola Adeleke ẹgbẹ oṣelu Accord, Bola Oyebamiji ẹgbẹ APC
Ati Najeem Salam ADC yoo ti maa takurọsọ lori erongba wọn fun ipinlẹ Osun
ẹ pade wa lori eto lọjọ Ẹti ọsẹ yii ọjọ kọkanlelọgbọn oṣe Keje

