Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Àkọlé fọ́nrán ohùn, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Published

Faakaja laarin ọlọpaa ati ileeṣẹ ọmogun oju omi

Ki lo dawọn pọ?

Ijoba ipinlẹ Ọsun lo maa fẹsun kan ileeṣẹ ọlọpaa pe wọn ṣekọlu sọmogun oju omi kan

To fọwọ omi mawọn janduku to n da ilu tori wọn fẹ gba gareeji ọkọ n'Ile-Ife

Ki ni ileeṣẹ ọlọpaa wa sọ?

Idahun sibeere rẹ wa loju opo wa

''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

A gbọdọ mọ ohun to ṣokunfa iku ọmọ wa

Ta lo tun ku?

Ijọba apapọ lo n pe fun iwadii kikun lori bi ọmọ Naijiria mi-in tun ṣeku sọwọ awọn ọlọpaa lorilẹede South Africa

Ọgbọnjọ oṣu Kẹfa to kọja yii ni South Africa fi gbedeke si

fawọn ajeji lati filuu wọn silẹ

Ẹkunrẹrẹ wa loju opo wa

''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Njẹ ẹ ti gbọ pe BBC Yoruba yoo ṣe ijiroro fawọn oludije sipo gomina nipinlẹ Osun

Nibi ijororo yii ni Gomina Ademola Adeleke ẹgbẹ oṣelu Accord, Bola Oyebamiji ẹgbẹ APC

Ati Najeem Salam ADC yoo ti maa takurọsọ lori erongba wọn fun ipinlẹ Osun

ẹ pade wa lori eto lọjọ Ẹti ọsẹ yii ọjọ kọkanlelọgbọn oṣe Keje