BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
04:11
Fídíò,
Bàbá mi ló pàṣẹ fún mi lójú àlá pé kí n máa múra bí ọkùnrin – Funmilayo Elemure Ogunyemi
, Duration 4,11
00:37
Fídíò,
Aráàlú fárígá, ṣèwọ́de ní Ibadan tako ìjọba lórí bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé ṣì ṣe wà ní àhámọ́
, Duration 0,37
02:45
Fídíò,
Ìfúpá àwọn èèyàn Ayetoro l‘Ondo ń ga sí, torí bí òkun ṣe ń ya wọ ìlú, gbé iléẹ̀kọ́, ilégbèé, iléeṣẹ́, ilẹ̀ àti ibojì òkù lọ
, Duration 2,45
01:26
Fídíò,
Wo àkóbá mọ́kànlá tí ohun mímu ‘Energy Drinks’ le ṣe fún àgọ́ ara rẹ
, Duration 1,26
04:32
Fídíò,
Ìjì òjò líle sí òrúlé, da ògiri wó nílé ẹ̀kọ́ girama ọgbọ̀n l‘Ogbomoso, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ n kẹ́kọ̀ọ́ lábẹ́ ilé àlàpa
, Duration 4,32
02:16
Fídíò,
"Ìjọba rí epo rọ̀bì ní ìlú wa àmọ́ a kò jàǹfààní kankan, kò sí omi, iná, ojú ọ̀nà, ààbò, iléẹ̀kọ́ àti ilé ìwòsàn"
, Duration 2,16
03:22
Fídíò,
Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele
, Duration 3,22
02:31
Fídíò,
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun
, Duration 2,31
02:34
Fídíò,
Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó
, Duration 2,34
02:21
Fídíò,
Olaniyan 'Idamu Industry' Oluwatosin jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí ètò 'Ṣé o láyà?'
, Duration 2,21
05:24
Fídíò,
Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá
, Duration 5,24
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Mo ní ipa tí mo lè kó láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, àmọ́, Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo ni kò gbàmí láyè - Igboho
4 Òkùdu 2026
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
4 Òkùdu 2026
Ṣé lóòótọ́ làwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso ti gbòmìnira? Ìjọba Oyo sọ̀rọ̀
4 Òkùdu 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?
28 Èbibi 2026
Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin
28 Èbibi 2026
Wo kókó ohun mọ́kànlá tí Tinubu fi ránṣẹ́ sọ́mọ Náíjíríà lórí ààbò àti ọrọ̀ ajé láti sàmì ọdún kẹta rẹ̀ nípò ààrẹ
29 Èbibi 2026
Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí
29 Èbibi 2026
Iran ṣàlàyé ìdí abájọ tó fi ṣèkọlù sí ibùdó ológun Amẹrika
29 Èbibi 2026
Kí ni pàtàkì Òkúta Dúdú táwọn olùjọsìn máa ń fọwọ́ kan tàbí fẹnu kò ní Kaaba lásìkò Hajj?
28 Èbibi 2026
Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe - Queen Mercy
29 Èbibi 2026
Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun
29 Èbibi 2026
Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam
26 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ṣé lóòótọ́ làwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso ti gbòmìnira? Ìjọba Oyo sọ̀rọ̀
2
Mo ní ipa tí mo lè kó láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, àmọ́, Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo ni kò gbàmí láyè - Igboho
3
Saheed Osupa, gbajúmọ̀ akọrin fuji ti pariwo síta lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso; ohun tó sọ rèé
4
Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun
5
INEC àti DSS bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lẹ́yìn tí àlàyé nípa olùdìbò lu síta lórí ayélujára
6
Yinka Alaseyori ṣàlàyé ara rẹ̀ lórí fídíò tó ṣe nípa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
7
Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí
8
Àwọn wo ló fẹ́ wú ère ẹlẹ́sẹ̀ ayò, Lionel Messi, àti pé kí ló fàá?
9
Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam
10
Agbébọn jí àbúrò mínísítà fún ohun àmúṣagbára tẹ́lẹ̀, Adebayo Adelabu àti ìbejì rẹ̀ gbé lọ ní Ibadan: ohun tí a mọ̀ rèé