Jeleosinmi Art Centre: Ibùdó yìí ló ń tọ́ ọ̀dọ́ sọ́nà nípa iṣẹ́ ọnà àti àṣà dípò ìwà àìda
Oniruuru awọn ibudo ikẹkọ lo wa paapaa fun awọn ogo wẹẹrẹ, lara rẹ ni ibudo Jeleosinmi tawọn ọmọde ti maa n kọkọ ẹkọ iwe.
Amọ ibudo ikẹkọ Jẹleosinmi ti Abolore Sobayo da silẹ yatọ nitori o n kọ awọn ọdọ ni ede Yoruba ati isẹ ọna lapapọ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori idi to fi da ibudo naa silẹ, Sobayo ni ọpọ ọdọ lo n fi ẹsẹ gbalẹ kiri, ti esu si n bẹ wọn nisẹ, lo mu ki oun da ibudo ti wọn yoo ti kọ nipa isẹ ọna ati asa wa silẹ.
- Abẹ́ tí wọ́n dá fún mí kò jẹ kí ìbálòpọ̀ wùnmi
- Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní
- Ṣé o rántí eré òṣùpá? Wo èré ìdárayá èyí tó yẹ fún àárọ̀ kùtù àti èyi tó wà fún òṣùpá
- A ti wẹ̀ rí sínú báàfù tí a wá fí alọ́ọ̀mù síi kí a tó mù ú lọ́jọ́ kéjí ní Kwara- Alhaji Saka
- Agbọ́nmágbọ́ntán, Agọ̀mágọ̀jù, mọ̀ síi nípa àwọn orúkọ Ìjàpá nínú alọ àpagbè Yorùbá
O fikun pe ọna lati fi pada fun awujọ ti oun ti jade wa, eyiun Oshodi, lo mu ki oun gbe ibudo jẹleosinmi naa kalẹ sibẹ.
Ni ibudo yii si ni awọn ọdọ ti n kọ nipa oniruuru ara ti wsn le fi isẹ ọna da ati ọpọ ohun to jẹ mọ asa wa nilẹ Yoruba.
Sobayo wa rọ awọn obi lati maa kọkọ fi ede abinibi kọ awọn ọmọ wọn nitori ko si anfaani ninu ki ọmọ wa ma gbọ ede wa.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn
- Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n
- Wo ìgbẹ̀yìn àwọn ọlọ̀tẹ̀ Yorùbá tó ran Fulani lọ́wọ́ láti kógun ja ìlú Osogbo
- Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu
- Ṣo mọ̀ pé J.F Odunjo jẹ aṣòfin àti mínísítà nílẹ̀ yìí, yàtọ̀ sí pé ó jẹ́ òǹkọ̀wé?
- Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa
- Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é



