Akomolede: Akuko Gagara ni ìwé tó ṣàfìhàn ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà lásìkò yìí- Fatimo Bola Owokunle
Published
Lere Adeyemi ṣe adape orukọ si Ajuba ati Aromire dipo Abuja ati Eko.
Iwe Akuko Gagara ti ko fẹ ki akukọ kekere mii kọ ni iwe ti a n gbeyẹwo lonii lori eto Akomolede ati aṣa lori BBC Yoruba.
Onkowe naa kọ iwe naa nipa fif ṣe afiwe ohun to n ṣẹlẹ laarin awọn oloselu, lọbaloba ati ara ilu Naijiria.
- Ẹ máa gbàá nìṣò, àwa Gómìnà ìhà Gúúsù f'ọwọ́ sí kí ìpínlẹ̀ má gba VAT
- Agbẹnusọ àjọ EFCC Wilson Uwujaren ti ṣàlàyé nǹkan tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọ̀gá àjọ náà lósàn ọjọ́bọ
- Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ni yóò parí ọ̀rọ̀ yìí -Ẹgbẹ́ àwọn Dókítà
- Eré ìfẹ́ di eré ẹkún! Olólùfẹ́ méjì lẹ̀pọ̀ lásìkò tí wọ́n n bá ara wọn sùn nínú adágún odò
- Àwọn agbẹ́bọn tí pa alága ẹgbẹ́ Miyetti Allah tí wọ́n jígbé ní Kaduna- Miyetti Allah
- Kí ẹnikẹ́ni má gbé ìyá mi síta mọ́, mí o ní agbẹnusọ kankan mọ́- Sunday Igboho
Itan in iwe naa ni o pa owe fun gbogbo awọn eeyan Naijiria ati oṣelu jẹgudujéra ti ko fẹ ki ọkan mékunnu balẹ.
Awọn afipagbajọba ati ipa awọn olowo lawujọ naa jẹ jade.

Alhaja Fatima Bola Owokunle lati ile ẹkọ Kwara State College of Arabic.
Itan naa lo ni awọn ẹda itan bii Dende, Alaasa to je igbakeji rẹ. Osoru ati bẹẹ bẹẹ lọ.
- Ojú ọjọ́ gbìgbóná jànyinjànyin ti kọjá kèrémí káàkiri àgbáyé
- Eré ìfẹ́ di eré ẹkún! Olólùfẹ́ méjì lẹ̀pọ̀ lásìkò tí wọ́n n bá ara wọn sùn nínú adágún odò
- Ọjọ́ tò burú jùlọ nínú ìrìnàjò oṣèlú mi ni ọjọ ti FFK darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC- Ojudu
- Agbẹnusọ àjọ EFCC Wilson Uwujaren ti ṣàlàyé nǹkan tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọ̀gá àjọ náà lósàn ọjọ́bọ
- Kí ẹnikẹ́ni má gbé ìyá mi síta mọ́, mí o ní agbẹnusọ kankan mọ́- Sunday Igboho





