Nanny: Èèyàn làwa náà, ẹ yé ṣe wá bí ẹranko
Published
Ọna lo jin, ẹru naa kuku ni baba.
Owe yii lo ṣalaye gẹlẹ bí awọn alagbatọ ninu fọnran yii ṣe ṣalaye bi awọn naa ṣe jẹ eeyan ti Ọlọrun da bii ẹlomiiran ṣugbọn ti awọn to gba wọn si iṣẹ maa n saba yi ero pada nipa wọn.
Awọn alagbatọ jẹ ko di mimọ pe bi kii ba ṣe bi awọn ọga to gba awọn ṣe n mu awọn ni, ko sohun to buru ninu ibaṣepọ to dan mọran.
Wọn jẹ ko di mimọ pe "ẹni to fẹ wa ba ẹ tọju ọmọ rẹ kan fẹran lati wa ran lọwọ ni".
Ẹwẹ, Pamela Akinboboye jẹ́ onímọ̀ nipa ìṣesí, o tẹnu bọ'rọ lori ohun ti eeyan le ṣe lati gbadun alagbatọ ọmọ rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
- Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà
- Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú...
- MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò
- Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè
- Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria
- Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin
- Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́...’ rèé