AFCON 2019: Bí Nàìjíríà ṣe gbá eyí tó lọ, mi ò lè sọ àsọtẹ́lẹ̀ti tònìí

Àkọlé fídíò, 'Bí Nàìjíríà ṣe gbá eyí tó lọ, mi ò lè sọ àsọtẹ́lẹ̀ti tònìí'
Published

Gẹgẹ bi awọn agbabọọlu Naijiria ṣe ti n gbara di fun ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹ̀lú ikọ agbabọọlu ti Cameroon, ọkan awọn ọmọ Naijiria naa ti wa loke.

Awọn ololufẹ ikọ super Eagles to n gbe orillẹ̀ede wọn larugẹ ni o yẹ ki awọn agbabọọlu gan ni imọ lara eyi ki wọn si lo gbogbo ọgbọn ati agbara ti wọn ba ni lati mu ori awọn ololufẹ wọn wu.

Bi awọn kan ṣe n sọ idi ti wọn ko fi ro pe Naijiria yoo bori Cameroon bẹẹ ni awọn mii n ṣa n fẹ́ẹ̀ ki Naijiria bori.

Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: