AFCON 2019: Debola olólùfẹ́ Super Eagles mú BBC Yorùbá dé ibùdó Bọ́ọ̀lù wíwò
Published
Ere Bọọlu jẹ ere idaraya kan ti awọn ọmọ Naijiria kii fi ṣere rara yala labẹle tabi lẹyin odi.
Bi idije ife ẹyẹ AFCON ṣe ti n lọ lọwọ ni Alexandria orilẹede Egypt, awọn ọmọ Naijiria ni awọn ọmọ Naijiria ṣe n tu jade lọ si ibudo iworan bọọlu.
Ọpọ ma n ri i pe eleyii ma n dun ju ki eeyan kan dede jokoo sinu ile lati da wo ifẹsẹwọnsẹ naa ayafi ti awọn ololufẹ bọọlu bii tiwọn ba wa nibẹ.
BBc Yoruba jade lati dara pọ mọ awọn ololufẹ ikọ Super Eagles lati jọ wo ifẹsẹwọnsẹ AFCON 2019 to n waye lọwọ lọwọ.
- Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
- Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà
- Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú...
- Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
- Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀
- Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè
- D.O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé
- Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.O Fágúnwà?
- Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú...