AFCON 2019: A bọ̀wọ̀ fún orílẹ̀èdè wa ju àwọn ikọ̀ míì tí à gba fún - Super Eagles
Published
Adari ikọ́ agbabọọlu Super Eagles, Genort Rohr atawọn ikọ agbabọọlu rẹ sọ ero wọn lori bi wọn ṣe ṣe e ti Madagascar mu wọn kọ oju awn ara Naijiria soorun alẹ.
Wọn si tun fọwọ sọya fun awọn ọmọ Naijiria pe awọn yoo ṣe ohun gbogbo to yẹ fun awọn ifsẹwọnsẹ to n bọ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí:
- Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin
- D.O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé
- Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀
- Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin
- Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà